Bá Ò kú | Rodiyah Ọmọ́tọ́yọ̀sí Mikail
Ṣóo wo iwájú tóò r’ẹ́nìkan O w’ẹ̀yìn wò, óò r’éèyàn L’ọ́tùn-ún l’ósì, ilẹ̀ tẹ́ lọ bẹẹrẹ Àṣẹ̀yìnwá àṣẹ̀yìnbọ̀, o ní […]
Ṣóo wo iwájú tóò r’ẹ́nìkan O w’ẹ̀yìn wò, óò r’éèyàn L’ọ́tùn-ún l’ósì, ilẹ̀ tẹ́ lọ bẹẹrẹ Àṣẹ̀yìnwá àṣẹ̀yìnbọ̀, o ní […]
Kókó omi ó ṣé ta, Bẹ́ ẹ̀ ni ọ̀pá tín-ín-rín ọrùn yìí ò ṣé é fà. Ẹkùn inú aginjù yí
Àgbà ọ̀pàpà paradà owó ará ìlú paradà ó dọbẹ̀ níkùn àgbà àgbà òṣèlú, àgbà ọ̀jẹ̀lú wọn jẹ̀lú jẹ̀lú, ìlú wó
Orí ire níí d’ádé owó Orùn ire níi s’èdìgbà ìlèkè Olóòtó ló ni ìgbádùn ayé Irú won ní sìí jè’gbádùn
Jòjòló akéwì tún dé Mo fẹ́ kọrin ewì sétí aráyé Ẹ yá mi létí yín. Ọ̀rọ̀ fẹ́ máa jábọ́ bí
Orin: Ẹnikẹ́ni tí ìwọ bá nípa láti se ìrànlọ́wọ́ fún Òun náà lẹni kejì rẹ, tọ́jú rẹ. Ẹnikẹ́ni tó bá
Ìbínú kò mọ̀ pé olówó òun ò lẹ́sẹ̀ ńlẹ̀. Ọ̀rẹ́ wa kan ló fi àṣejù kó bá ara rẹ̀ lẹ́nu
Ọ̀rọ̀ kan tí ń dùn mi lọ́kàn ọjọ́ pẹ́. Àsìkò tí tó wàyí tí n ó rò fáráalé. Ọ̀rọ̀ kan
Aáyan ògbufọ̀ iṣẹ́ “Àbíkú” láti ọwọ́ Wọlé Ṣóyínká Asán, òfúútù fẹ́ẹ̀tẹ̀, aásà tí kò ní kán-ún ni gbogbo ìlẹ̀kẹ̀ tí
Kò sẹ́ranko bí kìnnìún níjù. Bó dolókìtì ẹni tí ó ṣe bí ọ̀bọ ò sí. Ẹranko tí ó sọ pé