Àwọn Ìwé àti Dáyáàrì Sálù Jẹ́nwítèmi | ‘Gbénga Adéọba
I Ènìyàn bí reluwé ni Alàgbà Sálù Jẹ́nwítèmi; kò ṣeé kọlù, bẹ́ẹ̀ni kò sì gbọ́dọ̀ kọlu ènìyàn. Kì í see […]
I Ènìyàn bí reluwé ni Alàgbà Sálù Jẹ́nwítèmi; kò ṣeé kọlù, bẹ́ẹ̀ni kò sì gbọ́dọ̀ kọlu ènìyàn. Kì í see […]
Láti ìbẹ̀rẹ̀ pẹ̀pẹ̀, ọ̀kan gbòógì nínú ìdí tí a fi dá ÀTẸLẸWỌ sílẹ̀ ní ọdún 2017 ni títẹ ìwé jáde
Gbogbo rògbòdìyàn tó ń lọ ní’gboro tojú sú ni pátápátá.Tí t’ arúgbó t’omidan fi ń sá hílà-híloTí ìbẹ̀rù ìṣẹ́ òhun
Adé-ìmọ́lẹ̀ náà wúwo lórí ẹni mímọ́ náà, Ó rúnjúpọ̀ fún àpọ̀jù-ìmọ́lẹ̀tó wọ̀ ọ́ lójú, ó ti kó ṣáwùjọ̀ aláìrọ́runwọ̀. a
Ìfarajìn Fún D Eléyìí le wá sópin ní àwọn ọ̀nà méjì Pẹ̀lú rẹ, Mo fẹ́ èyí tó dára –Níbi tó
Igúnnugún bà lórùléOjú kálé, Ojú káko. Òrí akéwì kò ní jábọ́ Kó má yí nǹkan. Kí láǹfààní orógbó? A pa
Nígbà kan rí, àwọn ẹranko kéréjekéréje bi Eèrà, Ìjàlọ, Eku, Aáyán, Ikán àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ yan Ìjàlọ kó máa
Lati ọwọ́ọ Wálé Adébánwi, Akin Adéṣọ̀kàn, Tádé Ìpàdéọlá, Ebenezer Ọbádáre, àti Oyèníyì Òkúnoyè. Ni nǹkan bíi ọdún mẹ́fà sẹ́yìn ni
Ayé yìí ò le Pẹ̀lẹ́pẹ̀lẹ́ lejò ń gàgbọn. Ayé yìí ò gba gìrìgìrì Lọ̀gà fi ń tẹlẹ̀ jẹ́jẹ́jẹ́. Ẹ̀sọ̀ pẹ̀lẹ́
Ìtàn àròsọ yìí dálé ìtàn ìsẹ̀dálẹ̀ ìlú kan tí à ń pè ní ILÉ-OGBÓ ní Ìpínlẹ̀ Ọ̀sun, ILÉ-OGBÓ wà ní