Ẹnìkan Ò Layé àti ewì míràn | Ọládẹ̀jọ Hammed Ọ́
Ẹnìkan Ò Layé Ẹni ayé ńṣe maràba fún ó sọ́ra fẹ́nu aráyé Ẹ wí fún gbogbo molegòkè-molesọ̀ pé mo ní […]
Ẹnìkan Ò Layé Ẹni ayé ńṣe maràba fún ó sọ́ra fẹ́nu aráyé Ẹ wí fún gbogbo molegòkè-molesọ̀ pé mo ní […]
Ọmọ mí Mo bá wọn ná’jà Akẹ̀ẹ̀sán Mo bá wọn pé lọ́jà Orísúnbáre Ohun mò ń wá di tíntín abẹ́rẹ́
Mo lé téńté sórí igi odán mobojú wolẹ̀ láti wo àwọn ẹ̀dá tí Elédùmarè dá sílé Ayé À’teku, à’teye, àti
Ẹ Bọ̀wọ̀ F’ágbà “Ajá tó r’ólówó ẹ̀ rojú, kín ní ó f’ólówó è se kò tié yé mi.” —Éégunmọgají Àyìnlá
Nípa wíwà àti nínú Òfo Bó bá pẹ́ títí Ọmọ ènìyàn á ṣ’àfẹ́rí irẹ rẹ̀ lọ sí ònà jíjìn. Ó
Coro ló pojú kòró jẹ Ṣebí láti ọjọ́ táláyé ti dáyé L’ayé tí ń yí, tí ọmọ adáríhunrun ti ń
Apá Kiní Emọ́ kú ojú òpó dí Eésùn là, o là dànù Ọ̀pálánbá ọtí èèbó fọ́ Onígbá sọọ́ kò ri
Egbìrìn ọ̀tẹ̀ bí à ń ṣé pa ìkan ni ọ̀kan rú ní ìlú mi. Ní àgbàlá òdòdó yìí ẹ̀gún ń
Orí l’atọ́kùn ara, Olóòótọ́ tí ń darí ìwà, Awakọ̀ ti kii sìnà l’ójú ‘gbó, Orí mi gbé mi dé bi
À-pè-kánukò Àpèkánukò! Àpèṣ’ẹnu ṣùùtì Bí-i músù ú rẹ́ja nínú ike. Owó ní í jẹ́bẹ̀, ìwọ ọ̀rẹ́, Bí kò bá sí