Bí aré kò bá tó aré a kì í pòwe, bí ọ̀rọ̀ kò bá tọ́rọ̀ a kìí fìtàn balẹ̀, bí iṣẹ́ kò bá le a…
Kò sí ẹnì kankan tí kò mọ Ìyá àgbà ní abàá Alẹ́mọ́, kìí sọ ìtàn kan ní ẹ̀ẹ̀mejì. Àgbà òpìtàn sì ni pẹ̀lú. Kò fẹ́…
Ọ̀nà tí ó yá jù láti dá'ná sun ara ẹni Ni nípa fifi iná sí ilé ẹni. Òlùkọ́ èdè Gẹ̀ẹ́sì mi ló sọ wípé, Kí…
Olóko ń sun kún Oní igba ewùrà ló nù ní ódẹ̀ òhun Ará ilé mi ní: òhun ò l'oko, bẹ́ẹ̀ l'òhun ò ká ewùrà. Ará…
À ṣé àwọn tí wọn ń pé Àlàmú l’Ájá kò sọ àsọrégè rárá. Bí ó tí lẹ̀ jẹ́ pé àbísọ rẹ̀ ni nítorípé àbíkú ni.…
Kókó omi ó ṣé ta, Bẹ́ ẹ̀ ni ọ̀pá tín-ín-rín ọrùn yìí ò ṣé é fà. Ẹkùn inú aginjù yí wá di aláìléyíń, Ẹja rẹ̀…
ÀTẸ́LẸWỌ́ did this project to celebrate Bàbá Láwuyì Ògúnníran, the famous author of Eégún Aláré and many other Yorùbá literature books. We also did this…
Àgbà ọ̀pàpà paradà owó ará ìlú paradà ó dọbẹ̀ níkùn àgbà àgbà òṣèlú, àgbà ọ̀jẹ̀lú wọn jẹ̀lú jẹ̀lú, ìlú wó wọn jẹ̀lú jẹ̀lú, ìlú lu.…
Orí ire níí d'ádé owó Orùn ire níi s'èdìgbà ìlèkè Olóòtó ló ni ìgbádùn ayé Irú won ní sìí jè'gbádùn ayé L'élé báyìí ni oká…
Jòjòló akéwì tún dé Mo fẹ́ kọrin ewì sétí aráyé Ẹ yá mi létí yín. Ọ̀rọ̀ fẹ́ máa jábọ́ bí odi ẹyìn. Kí ẹ sáré…