Òpóǹló ni mo wà tí mo ti máa ń gbọ́ nípa ìlú Èkó. Oríṣiríṣi ni atilẹ̀ máa ń gbọ́ ni ìgbà náà. Àwọn kan àtilẹ̀…
Kókó omi ó ṣé ta, Bẹ́ ẹ̀ ni ọ̀pá tín-ín-rín ọrùn yìí ò ṣé é fà. Ẹkùn inú aginjù yí wá di aláìléyíń, Ẹja rẹ̀…
ÀTẸ́LẸWỌ́ did this project to celebrate Bàbá Láwuyì Ògúnníran, the famous author of Eégún Aláré and many other Yorùbá literature books. We also did this…
Àgbà ọ̀pàpà paradà owó ará ìlú paradà ó dọbẹ̀ níkùn àgbà àgbà òṣèlú, àgbà ọ̀jẹ̀lú wọn jẹ̀lú jẹ̀lú, ìlú wó wọn jẹ̀lú jẹ̀lú, ìlú lu.…
Orí ire níí d'ádé owó Orùn ire níi s'èdìgbà ìlèkè Olóòtó ló ni ìgbádùn ayé Irú won ní sìí jè'gbádùn ayé L'élé báyìí ni oká…
Jòjòló akéwì tún dé Mo fẹ́ kọrin ewì sétí aráyé Ẹ yá mi létí yín. Ọ̀rọ̀ fẹ́ máa jábọ́ bí odi ẹyìn. Kí ẹ sáré…
Orin: Ẹnikẹ́ni tí ìwọ bá nípa láti se ìrànlọ́wọ́ fún Òun náà lẹni kejì rẹ, tọ́jú rẹ. Ẹnikẹ́ni tó bá nípa láti ṣe ìrànwọ́ fún…
Ìbínú kò mọ̀ pé olówó òun ò lẹ́sẹ̀ ńlẹ̀. Ọ̀rẹ́ wa kan ló fi àṣejù kó bá ara rẹ̀ lẹ́nu ọjọ́ mẹ́ta yìí. Ó ń…
Eerin wó, Àjànàkú sùn bí òkè! O ṣe ni láàánú gidigidi láti gbọ́ pé Bàbá Láwuyì Ògúnníran, ọ̀kan gbòógí nínú àwọn òǹkọ̀we Yorùbá pa ‘po…
Ọ̀rọ̀ kan tí ń dùn mi lọ́kàn ọjọ́ pẹ́. Àsìkò tí tó wàyí tí n ó rò fáráalé. Ọ̀rọ̀ kan tí ń ṣe mí ní…